Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ ikọ̀ Boko Haram tàbí lọ bá àwọn ọlọ́ṣà agbésùmọ́mí fún ijiroro ìpàdé àlàáfíà , gẹ́gẹ́ bí Jonathan àti Osinbajo ti ṣe pẹ̀lú àwọn ọlọ̀tẹ̀ oníjàgídíjàgan agbègbè Niger Delta (Niger Delta militants) .

Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ…

Ka siwaju

Ọmọ ẹni ti o da ile-iṣẹ ọ̀kín bisikiiti silẹ sọrọ nipa iroyin ipadabọ awọn bisikiiti OkinIle-iṣẹ Okin Industries sọ pe awọn ṣe ìgbìyànjú lati tun mu ami-ọja bisikiiti Okin ti o gbajumọ pada wa si ipo rẹ ṣi n lọ lọwọ, eyi ti o n funni ni ireti pe yoo pada wa si orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ọpọlọpọ ti n reti rẹ láìpẹ́ .

Ọmọ ẹni ti o da ile-iṣẹ naa silẹ sọrọ nipa iroyin ipadabọ awọn bisikiiti OkinIle-iṣẹ Okin Industries sọ pe awọn…

Ka siwaju