Ó pọn dandan fún APC láti borí nínú ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun,’ Alága Àpapọ̀ sọ bẹ́ẹ̀; ó ní wọn yóò kó àwọn Gómìnà, àwọn Àgbà-òjíṣẹ́, àti àwọn mìíràn wá láti kópa nínú ìdìbò náà.’A gbọ́dọ̀ borí nínú ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun fún ẹgbẹ́ APC,’ ni Alága Orílẹ̀-èdè sọ; yóò sì kó àwọn Gómìnà, àwọn Mínísítà, àti àwọn mìíràn wá láti kópa nínú ìdìbò náà.

Ó pọn dandan fún APC láti borí nínú ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun,’ Alága Àpapọ̀ sọ bẹ́ẹ̀; ó ní wọn yóò kó…

Ka siwaju

Gómìnà Ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ Seyi Makinde ni àárọ̀ òní tíì ṣe ọjọ́ Àbámẹ́ta, Ọgbọ̀n ọjọ́ Oṣù Kàrún 2026, kó Ọgọọgọrun àwọn ọkọ̀ ayọkẹlẹ tí ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn irinṣẹ ìbániẹnisọ̀rọ̀ fún àwọn ilé isẹ ààbò ni ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá.

Gómìnà Ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ Seyi Makinde ni àárọ̀ òní tíì ṣe ọjọ́ Àbámẹ́ta, Ọgbọ̀n ọjọ́ Oṣù Kàrún 2026, kó Ọgọọgọrun àwọn…

Ka siwaju