Skip to content
  • Tuesday, 30 June 2026
  • 4:34 pm
  • Tẹle wa
ÀṢÀKẸ́ NEWS
  • Ile
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • Ẹ̀KỌ́ ÈDÈ YORÙBÁ
  • Home
  • Ìyá àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin pàdánù ẹ̀mí wọn bí wọn ṣe n rin ìrìn àjò lọ sí ilẹ̀ mímọ́ Mecca.
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Ìyá àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin pàdánù ẹ̀mí wọn bí wọn ṣe n rin ìrìn àjò lọ sí ilẹ̀ mímọ́ Mecca.

Asake Apr 22, 2026 0

Àwọn Àjọ tó ń ṣe agbeteru ìrìnàjò lọ sí ilẹ̀ mímọ́ Mecca tí ìpínlẹ̀ Kano pilgrim tí kẹ́dùn ìyá àti…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí pa àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà mẹrin jí ọ̀pọ̀ ará ìlú gbé lọ, ni ọgbà ológun kemanji Kwara.

Asake Apr 20, 2026 0

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí da ìbọn bolẹ̀ yawọ ọgbà àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà tó wà ní kemanji ni ijoba ìbílẹ̀ kaiama Kwara,…

Ka siwaju
ÌGBÉSÍ AYÉ Uncategorized

Lebanon yẹ àdéhùn jógunómí ọlọ́sẹ̀ méjì, wọ́n ju àdó olóró sí Israel.

Asake Apr 19, 2026 1

Àlàyé tí Netanyahu ṣe rèé lórí àdéhùn jógunómí tó wà láàrin Israeli àti Lebanon Àdéhùn jógunómí yìí bá ọ̀pọ̀ ọmọ…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Ìjọba àpapọ̀ tí rán àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà igba (200)lọ sí Turkey láti lọ kọ́ iṣẹ́ ogun jíjà láti lè kojú àwọn agbéṣùmọ̀mí.

Asake Apr 19, 2026 0

Ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà tí kó àwọn ọmọ ogun igba (200) ránṣẹ́ lọ sí Turkey láti lọ kọ́ ìjà ogun jíjà…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ọba onípele tí ipele Ọ̀wọ̀ ń dunkoko ikú mọ́ ọmọbìnrin ọdún mọ́kànlélógún (21yrs),Látàrí bí Kehinde ṣe sọ pé ọba lo fún òun lóyún tí ọba sì ní kí òun ló yọ oyún náà, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, òun yóò fi ikú ṣe ifá jẹ́.

Asake Apr 18, 2026 6

Ọba onípele tí ipele ni ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀wọ́ Ondo ń dunkoko ikú mọ́ ọmọ ọdún mọ́kànlélógún (21yrs) tí orúkọ rẹ…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn ìdílé òye méjì Fagbemirokun àti Aribile fún ìjọba Ọ̀sun ní gbèdéke ọjọ́ méje láti rọ ọba Ipetumodu Oloyede tó wà lẹ́wọ̀n L’ámẹ́ríkà lóyè.

Asake Apr 17, 2026 0

Àwọn ìdílé ọmọ òye Fagbemirokun àti Aribile fún ìjọba Ọ̀sun ní gbèdéke ọjọ́ méje péré láti rọ Apetu tí Ipetumodu…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Ọmọ Nàìjíríà tó wà ní UK, Adewale Anthony Sobogun ẹni ọdún (61yrs)rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n(28yrs ) he, fún ẹ̀sùn ìfipábá ọmọdébìnrin méjì lò pọ̀.

Asake Apr 17, 2026 0

Adewale Sobogun jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́ta, tí ó sì ti ń gbé orílẹ̀ èdè Biritiko( Uk) ti pẹ́. Ilé ẹjọ́…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Èyí ni àwọn ohun tí olórí ìjọ Aguda póòpù Leo xiv wá ṣe ni ilẹ̀ Adúláwò :Algeria, Cameron, Angola…

Asake Apr 16, 2026 0

Àmí àlàáfíà àti ìrètí ni póòpù jẹ́, ìpẹ̀tùsááwọ̀ káàkiri àgbáyé. Ní ọjọ́ Ajé, ọjọ́ kẹtàlá oṣù kẹrin ọdún 2026 ni…

Ka siwaju
ÌṢÈLÚ

Ọba olubadan Ladoja ń pète-pèrò láti yọ gómìnà Ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ Seyi Makinde.Ọ̀rọ̀ ń bọ́rọ̀ ń bọ̀ eégún aláré..

Asake Apr 16, 2026 1

Ayode Fayose kọ̀jálẹ̀ pé ọ̀rọ̀ tí ó ń sọ pé Seyi Makinde fẹ́ yọ Olubadan Ọba Abdulrasheed Adewolu Ladoja kúrò…

Ka siwaju
ÌṢÈLÚ

Nítorí ọ̀rọ̀ ìdìbò2027 tó ń bọ̀ lọ́nà ni ó fa àìsí ètò àbò tó ń peléke si, tí ìdìbò bá ti parí,ẹ kò ní gbúrò àdó olóró mọ́.

Asake Apr 15, 2026 0

Nítorí ọ̀rọ̀ ìdìbò2027 tó ń bọ̀ lọ́nà ni ó faàìsí ètò àbò tó ń peléke si, tí ètò idibò bá…

Ka siwaju

Posts pagination

1 … 8 9 10 11

Iroyin aipẹ

  • Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
  • Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
  • Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
  • Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
  • Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Iroyin to Nlo
Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
Jun 30, 2026
Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
Jun 29, 2026
Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Jun 29, 2026

Asọye aipẹ

  1. Katie1486 on Ìpayà bí iná ṣe jó ilé ìtajà ike tó wà ni old garage Osogbo tó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀sun.
  2. Hello from [your-website] on Bokoharam kéde pé àwọn fẹ́ ṣe ayẹyẹ ìparí ẹ̀kọ́ Al-Quran fún ọgọ́rùn-ún (100) nínú àwọn obìnrin àti àwọn ọmọ tí wọ́n jí gbé ní ìjọba Kaiama Kwara I to tí kẹ́kọ̀ọ́ yege ni àhámọ́ wọn.
  3. Asake on Ìjọba àpapọ̀ tí kó orúkọ àwọn ọmọ Nàìjíríà síta ,Tukur Mamu, Simon Njoku Ekpa, IPOB, àti àwọn gúrúpù12 mìíràn, tó ń ṣe ìrànlọ́wọ́ àti àtìlẹyìn fún àwọn agbésùnmọ̀mí.
  4. Asake on Ọwọ́ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó ti tẹ ọlọ́pàá tó n gba owó rìbá lọ́wọ́ àwọn awakọ̀, onikẹ̀kẹ́ maruwa, ọlọ́kadà ní Idimu L’eko.
  5. Asake on Ààrẹ Tinubu buwọ́lu N17bilionu láti ṣe àtìlẹyìn ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀,àti àwọn agbègbè ìsèlù 8,804 gbogbo orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Iroyin ti oti le Ti padanu
News Mart logo

Ni pa wa

Shagam
info@asakenews.com
+212 710-380820
Iroyin Tuntun
Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
Jun 30, 2026
Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
Jun 29, 2026
Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Jun 29, 2026
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Forukọsilẹ Fun Iwe Iroyin Wa

Se alabapin si iwe iroyin wa lati gba awọn nkan tuntun wa lesekese!

Copyright © 2026 Asake News | Design by Yaagboyaaju Tech

  • Home
  • About
  • Blog
  • Contact