Skip to content
  • Sunday, 16 August 2026
  • 6:18 pm
  • Tẹle wa
ÀṢÀKẸ́ NEWS
  • Ile
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • Ẹ̀KỌ́ ÈDÈ YORÙBÁ
  • Home
  • Oyedepo kéde ìdájọ́ lórí àwọn olugbowo to ń ṣe àtìlẹyìn fún àwọn agbésùnmọ̀mí
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Oyedepo kéde ìdájọ́ lórí àwọn olugbowo to ń ṣe àtìlẹyìn fún àwọn agbésùnmọ̀mí

Asake Apr 23, 2026 0

Olùdásílè ti ìjọ Living Faith Church Worldwide, Bishop David Oyedepo, ti kéde ìdájọ́ lórí àwọn Adigunjalè,agbésùnmọ̀mí afẹ̀míṣòfòati awọn onígbọ̀wọ́ wọn.Oyedepo…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Abdrahman kéde pé òun yóò san N20milionu fún ẹnì kọ̀ọ̀kan àwọn ológun mẹta tí àwọn agbésùnmọ̀mí pa ni ọgbà ológun kemanji Kwara.

Asake Apr 21, 2026 0

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Abdrahman tí ṣe ìpinnu pé òun yóò san N20m fún ẹnì kọ̀ọ̀kan àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà mẹta…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí pa àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà mẹrin jí ọ̀pọ̀ ará ìlú gbé lọ, ni ọgbà ológun kemanji Kwara.

Asake Apr 20, 2026 0

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí da ìbọn bolẹ̀ yawọ ọgbà àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà tó wà ní kemanji ni ijoba ìbílẹ̀ kaiama Kwara,…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn ìdílé òye méjì Fagbemirokun àti Aribile fún ìjọba Ọ̀sun ní gbèdéke ọjọ́ méje láti rọ ọba Ipetumodu Oloyede tó wà lẹ́wọ̀n L’ámẹ́ríkà lóyè.

Asake Apr 17, 2026 0

Àwọn ìdílé ọmọ òye Fagbemirokun àti Aribile fún ìjọba Ọ̀sun ní gbèdéke ọjọ́ méje péré láti rọ Apetu tí Ipetumodu…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Ọmọ Nàìjíríà tó wà ní UK, Adewale Anthony Sobogun ẹni ọdún (61yrs)rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n(28yrs ) he, fún ẹ̀sùn ìfipábá ọmọdébìnrin méjì lò pọ̀.

Asake Apr 17, 2026 0

Adewale Sobogun jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́ta, tí ó sì ti ń gbé orílẹ̀ èdè Biritiko( Uk) ti pẹ́. Ilé ẹjọ́…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ìjọba àpapọ̀ tí kó orúkọ àwọn ọmọ Nàìjíríà síta ,Tukur Mamu, Simon Njoku Ekpa, IPOB, àti àwọn gúrúpù12 mìíràn, tó ń ṣe ìrànlọ́wọ́ àti àtìlẹyìn fún àwọn agbésùnmọ̀mí.

Asake Apr 12, 2026 2

Ìjọba àpapọ̀ tí kó gbogbo orúkọ àwọn ọmọ Nàìjíríà síta ,lára wọn ni Tukur Mamu, Simon Njoku Ekpa,tí ó jẹ…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ènìyàn márùn ni àwọn agbesunmobi tún ti pa lára wọn ni T. Dollar, ní Igbatoro ni ìpínlẹ̀ Ondo, Àwọn ará ìlú gbegi di òpópónà ọ́fíìsí Gómìnà ni Akure.

Asake Apr 11, 2026 0

Àwọn ará ìlú se ìfẹ̀hónúhàn láti ké gbàjarè sì etí ìjọba bí àwọn agbesunmobi ṣe n pa àwọn ènìyàn lójoojúmọ́…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Olórí Ọlọ́dẹ àti àwọn Aṣọ́gbó márùn-ún pàdánù ẹ̀mí wọn ni Kwara bí àwọn agbesunmobi ṣe yabo wọn, tí wọ́n sì dáná sún ọkọ̀ àti ọ̀kadà wọn.

Asake Apr 10, 2026 3

Fọ́nrán àti àwòrán tó jáde síta ṣe àfihàn bí àwọn agbesunmobi ṣe dáná sún ọkọ̀ àti ọ̀kadà àwọn Aṣọ́gbó náà,…

Ka siwaju
ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn agbesunmobi yawọ oko ọ̀sìn Adìẹ, wọn yinbon pa ìyá tó ni ọ̀sìn Adìẹ náà àti ọmọ rẹ̀ obìnrin ni agbègbè Igushin Ala Akure North (apá Àríwá Akure)

Asake Apr 10, 2026 3

Àwọn agbesunmobi yinbon pa ìyá àti ọmọ rẹ̀ obìnrin lójú ẹsẹ bí wọ́n ṣe yawọ inú oko ọ̀sìn Adìẹ ni…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí Bokoharam tún ti pa ọ̀gágun O. Braimah lénu isẹ́ bí wọn ṣe ṣe ìkọlù sí ọgbà ológun Benisheikh Borno

Asake Apr 9, 2026 0

Àwọn agbesunmobi ikọ̀ bokoharam pa Ọ̀gágún O. Braimah Alakoso ẹgbẹ́ ọmọ ogún Naijiria tì o jẹ́ ẹ̀ka 29 ikọ̀ ọgbà…

Ka siwaju

Posts pagination

1 … 4 5

Iroyin aipẹ

  • Ìdìbò ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Obìnrin oníwà-ipá jàǹdùnkú olóṣèlú kan tí wọ́n ń pè ní ‘Arugba’ halẹ̀ mọ́ àwọn olùdìbò pé òun yóò gé ìka ọwọ́ wọn tí wọn kò bá dìbò fún ẹgbẹ́ APC.
  • Ikọlu sí Agbẹnusọ Ile-igbimọ Ipinle Osun: Afurasi jẹwọ pe oludije ẹgbẹ APC, Eniade, lo gba oun láti pa a, o si tun jẹwọ pe oun yin ibọn lẹẹmeji.
  • Amnesty International tún rọ àwọn aláṣẹ ní Nàìjíríà láti bọ̀wọ̀ fún àwọn ẹ̀tọ́ ọmọ-ìlú nígbà ìdìbò Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
  • Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Àwọn ọlọ́pàá pe Sẹ́nátọ̀ Fadahunsi ti ẹgbẹ́ APC wá fún ìbéèrè lórí ọ̀rọ̀ ìhalẹ̀ láti pa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Accord.
  • Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Adeleke, fi ẹ̀sùn kan àwọn ọlọ́pàá pé wọ́n ní ètò láti mú àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord kí wọ́n sì fi wọ́n sẹ́wọ̀n ní Abuja títí tí ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun yóò fi parí.
Iroyin to Nlo
Ìdìbò ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Obìnrin oníwà-ipá jàǹdùnkú olóṣèlú kan tí wọ́n ń pè ní ‘Arugba’ halẹ̀ mọ́ àwọn olùdìbò pé òun yóò gé ìka ọwọ́ wọn tí wọn kò bá dìbò fún ẹgbẹ́ APC.
Aug 13, 2026
Ikọlu sí Agbẹnusọ Ile-igbimọ Ipinle Osun: Afurasi jẹwọ pe oludije ẹgbẹ APC, Eniade, lo gba oun láti pa a, o si tun jẹwọ pe oun yin ibọn lẹẹmeji.
Aug 13, 2026
Amnesty International tún rọ àwọn aláṣẹ ní Nàìjíríà láti bọ̀wọ̀ fún àwọn ẹ̀tọ́ ọmọ-ìlú nígbà ìdìbò Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
Aug 12, 2026
Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Àwọn ọlọ́pàá pe Sẹ́nátọ̀ Fadahunsi ti ẹgbẹ́ APC wá fún ìbéèrè lórí ọ̀rọ̀ ìhalẹ̀ láti pa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Accord.
Aug 12, 2026
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Adeleke, fi ẹ̀sùn kan àwọn ọlọ́pàá pé wọ́n ní ètò láti mú àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord kí wọ́n sì fi wọ́n sẹ́wọ̀n ní Abuja títí tí ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun yóò fi parí.
Aug 12, 2026

Asọye aipẹ

  1. ABDULRASAQ ADENIYI SOLIU on Àwọn ọkùnrin mẹ́jọ tí ọjọ́ orí wọn wà láàárín ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún sì méjìlélọ́gbọ̀n ni wọ́n fi ẹ̀sùn kàn lórí ètò láti kọlu ayẹyẹ UFC ti Trump ní Ilé Ààrẹ ni White House.
  2. Lewishow on Ìpayà bí iná ṣe jó ilé ìtajà ike tó wà ni old garage Osogbo tó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀sun.
  3. Timsothyemeri on Ìpayà bí iná ṣe jó ilé ìtajà ike tó wà ni old garage Osogbo tó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀sun.
  4. OLUFEMI OSHIKPOYA on Wọn pa ènìyàn kan, ọpọlọpọ farapa yannayanna bí Ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti Accord Party ṣe ja ni Osogbo.
  5. Alma1848 on Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ẹdo tẹ afurasí ajínigbé méjì, wọn gba ara ènìyàn tó ti jẹrà méjì padà.
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Iroyin ti oti le Ti padanu
News Mart logo

Ni pa wa

Shagam
info@asakenews.com
+212 710-380820
Iroyin Tuntun
Ìdìbò ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Obìnrin oníwà-ipá jàǹdùnkú olóṣèlú kan tí wọ́n ń pè ní ‘Arugba’ halẹ̀ mọ́ àwọn olùdìbò pé òun yóò gé ìka ọwọ́ wọn tí wọn kò bá dìbò fún ẹgbẹ́ APC.
Aug 13, 2026
Ikọlu sí Agbẹnusọ Ile-igbimọ Ipinle Osun: Afurasi jẹwọ pe oludije ẹgbẹ APC, Eniade, lo gba oun láti pa a, o si tun jẹwọ pe oun yin ibọn lẹẹmeji.
Aug 13, 2026
Amnesty International tún rọ àwọn aláṣẹ ní Nàìjíríà láti bọ̀wọ̀ fún àwọn ẹ̀tọ́ ọmọ-ìlú nígbà ìdìbò Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
Aug 12, 2026
Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Àwọn ọlọ́pàá pe Sẹ́nátọ̀ Fadahunsi ti ẹgbẹ́ APC wá fún ìbéèrè lórí ọ̀rọ̀ ìhalẹ̀ láti pa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Accord.
Aug 12, 2026
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Adeleke, fi ẹ̀sùn kan àwọn ọlọ́pàá pé wọ́n ní ètò láti mú àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord kí wọ́n sì fi wọ́n sẹ́wọ̀n ní Abuja títí tí ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun yóò fi parí.
Aug 12, 2026
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Forukọsilẹ Fun Iwe Iroyin Wa

Se alabapin si iwe iroyin wa lati gba awọn nkan tuntun wa lesekese!

Copyright © 2026 Asake News | Design by Yaagboyaaju Tech

  • Home
  • About
  • Blog
  • Contact