Skip to content
  • Tuesday, 30 June 2026
  • 2:06 pm
  • Tẹle wa
ÀṢÀKẸ́ NEWS
  • Ile
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • Ẹ̀KỌ́ ÈDÈ YORÙBÁ
  • Home
  • Archive by category "ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ"
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

A kò fi ìwé pé Sultan Sokoto síbi ayẹyẹ ibi tí a ti fẹ́ ṣí pápákọ̀ òfuurufú Chapel tuntun ní Fct Labuja -CAN

Asake Apr 19, 2026 3

Àpapọ̀ aṣojú ẹlẹ́sìn Kìrìsìtẹ́nì(CAN) sọ pé àwọn kò fi ìwé pé Sultan Sokoto Sa’ad Abubakar, láti wá ṣe bí adarí…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ọba onípele tí ipele Ọ̀wọ̀ ń dunkoko ikú mọ́ ọmọbìnrin ọdún mọ́kànlélógún (21yrs),Látàrí bí Kehinde ṣe sọ pé ọba lo fún òun lóyún tí ọba sì ní kí òun ló yọ oyún náà, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, òun yóò fi ikú ṣe ifá jẹ́.

Asake Apr 18, 2026 6

Ọba onípele tí ipele ni ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀wọ́ Ondo ń dunkoko ikú mọ́ ọmọ ọdún mọ́kànlélógún (21yrs) tí orúkọ rẹ…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ọwọ́ tí tẹ àwọn arákùnrin méjì tó lọ hu agbari òkú nínú saare láti fi jogún ni Kwara.

Asake Apr 17, 2026 0

Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara tẹ arakunrin tó gbé agbari òkú pamọ sí inú saka gaari tó fẹ́ fi joogun pẹ̀lú…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn ìdílé òye méjì Fagbemirokun àti Aribile fún ìjọba Ọ̀sun ní gbèdéke ọjọ́ méje láti rọ ọba Ipetumodu Oloyede tó wà lẹ́wọ̀n L’ámẹ́ríkà lóyè.

Asake Apr 17, 2026 0

Àwọn ìdílé ọmọ òye Fagbemirokun àti Aribile fún ìjọba Ọ̀sun ní gbèdéke ọjọ́ méje péré láti rọ Apetu tí Ipetumodu…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ọwọ́ tí tẹ àwọn agbésùnmọ̀mí 33 tí wón ṣe ìkọlù sí Ilé ìjọsìn CAC òkè ìṣẹ́gun Eruku Kwara .

Asake Apr 15, 2026 0

Tí ẹ bá ní gbàgbé, ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kọkànlá ọdún 2025, ní àwọn agbesunmobi yawọ ilé ìjọsìn CAC òkè…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn fulani darandaran pa olóyè ọ̀tún Balógun oluode Mutairu Oladosu ti okelade Ido Ìbàdàn sínú oko tomato rẹ̀.

Asake Apr 14, 2026 1

Àwọn fulani agbésùnmọ̀mí darandaran pa olóyè Otun Balógun Oluode Okelade ni Ìbàdàn.Ọba Wahab Olabamiji ti Okelade Ibadan lo fi idi…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Seyi Makinde fẹ́ yọ Olubadan Ọba Abdulrasheed Adewolu Ladoja kúrò lórí ìtẹ́

Asake Apr 12, 2026 2

Àtẹ̀jáde kan tí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀ rí, Ayodele Fayose fi sí orí ìkànnì ayélujára abẹ́yẹfò x rẹ, lo tí…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ìjọba àpapọ̀ tí kó orúkọ àwọn ọmọ Nàìjíríà síta ,Tukur Mamu, Simon Njoku Ekpa, IPOB, àti àwọn gúrúpù12 mìíràn, tó ń ṣe ìrànlọ́wọ́ àti àtìlẹyìn fún àwọn agbésùnmọ̀mí.

Asake Apr 12, 2026 2

Ìjọba àpapọ̀ tí kó gbogbo orúkọ àwọn ọmọ Nàìjíríà síta ,lára wọn ni Tukur Mamu, Simon Njoku Ekpa,tí ó jẹ…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ẹ gba ìwé ìrìnnà lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni tí ó bá ní òun kì í ṣe ọmọ Nàìjíríà mọ́, mínísítà ọ̀rọ̀ abẹ́lé Tunji Ojo pàṣẹ fún iléeṣẹ́ tó ń rí sí ìwọlé – jáde Nàìjíríà

Asake Apr 12, 2026 0

Ìjọba àpapọ̀ tí fi òfin tuntun lélẹ̀, ẹnikẹ́ni tí ó bá ní òun kii se ọmọ Nàìjíríà mọ̀ ọ́, ijọba…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ènìyàn márùn ni àwọn agbesunmobi tún ti pa lára wọn ni T. Dollar, ní Igbatoro ni ìpínlẹ̀ Ondo, Àwọn ará ìlú gbegi di òpópónà ọ́fíìsí Gómìnà ni Akure.

Asake Apr 11, 2026 0

Àwọn ará ìlú se ìfẹ̀hónúhàn láti ké gbàjarè sì etí ìjọba bí àwọn agbesunmobi ṣe n pa àwọn ènìyàn lójoojúmọ́…

Ka siwaju

Posts pagination

1 … 11 12 13

Iroyin aipẹ

  • Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
  • Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
  • Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
  • Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
  • Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Iroyin to Nlo
Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
Jun 30, 2026
Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
Jun 29, 2026
Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Jun 29, 2026

Asọye aipẹ

  1. Katie1486 on Ìpayà bí iná ṣe jó ilé ìtajà ike tó wà ni old garage Osogbo tó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀sun.
  2. Hello from [your-website] on Bokoharam kéde pé àwọn fẹ́ ṣe ayẹyẹ ìparí ẹ̀kọ́ Al-Quran fún ọgọ́rùn-ún (100) nínú àwọn obìnrin àti àwọn ọmọ tí wọ́n jí gbé ní ìjọba Kaiama Kwara I to tí kẹ́kọ̀ọ́ yege ni àhámọ́ wọn.
  3. Asake on Ìjọba àpapọ̀ tí kó orúkọ àwọn ọmọ Nàìjíríà síta ,Tukur Mamu, Simon Njoku Ekpa, IPOB, àti àwọn gúrúpù12 mìíràn, tó ń ṣe ìrànlọ́wọ́ àti àtìlẹyìn fún àwọn agbésùnmọ̀mí.
  4. Asake on Ọwọ́ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó ti tẹ ọlọ́pàá tó n gba owó rìbá lọ́wọ́ àwọn awakọ̀, onikẹ̀kẹ́ maruwa, ọlọ́kadà ní Idimu L’eko.
  5. Asake on Ààrẹ Tinubu buwọ́lu N17bilionu láti ṣe àtìlẹyìn ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀,àti àwọn agbègbè ìsèlù 8,804 gbogbo orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Iroyin ti oti le Ti padanu
News Mart logo

Ni pa wa

Shagam
info@asakenews.com
+212 710-380820
Iroyin Tuntun
Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
Jun 30, 2026
Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
Jun 29, 2026
Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Jun 29, 2026
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Forukọsilẹ Fun Iwe Iroyin Wa

Se alabapin si iwe iroyin wa lati gba awọn nkan tuntun wa lesekese!

Copyright © 2026 Asake News | Design by Yaagboyaaju Tech

  • Home
  • About
  • Blog
  • Contact