Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ ikọ̀ Boko Haram tàbí lọ bá àwọn ọlọ́ṣà agbésùmọ́mí fún ijiroro ìpàdé àlàáfíà , gẹ́gẹ́ bí Jonathan àti Osinbajo ti ṣe pẹ̀lú àwọn ọlọ̀tẹ̀ oníjàgídíjàgan agbègbè Niger Delta (Niger Delta militants) .

Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ…

Ka siwaju

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá mú àwọn òṣìṣẹ́ ọlọ́pàá mẹ́rin lẹ́yìn tí fídíò wọn jáde sórí ayélujára tó fi ẹ̀tanú ẹlẹ́yàmẹyà hàn, fa ìbínú gbígbóná janjan, tí wọ́n sì ń bèrè owo lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà tó ń bọ̀ láti UK.

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá mú àwọn òṣìṣẹ́ ọlọ́pàá mẹ́rin lẹ́yìn tí fídíò wọn jáde sórí ayélujára tó fi ẹ̀tanú ẹlẹ́yàmẹyà hàn, fa…

Ka siwaju