Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ ikọ̀ Boko Haram tàbí lọ bá àwọn ọlọ́ṣà agbésùmọ́mí fún ijiroro ìpàdé àlàáfíà , gẹ́gẹ́ bí Jonathan àti Osinbajo ti ṣe pẹ̀lú àwọn ọlọ̀tẹ̀ oníjàgídíjàgan agbègbè Niger Delta (Niger Delta militants) .

Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ…

Ka siwaju

Ọmọ ẹni ti o da ile-iṣẹ ọ̀kín bisikiiti silẹ sọrọ nipa iroyin ipadabọ awọn bisikiiti OkinIle-iṣẹ Okin Industries sọ pe awọn ṣe ìgbìyànjú lati tun mu ami-ọja bisikiiti Okin ti o gbajumọ pada wa si ipo rẹ ṣi n lọ lọwọ, eyi ti o n funni ni ireti pe yoo pada wa si orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ọpọlọpọ ti n reti rẹ láìpẹ́ .

Ọmọ ẹni ti o da ile-iṣẹ naa silẹ sọrọ nipa iroyin ipadabọ awọn bisikiiti OkinIle-iṣẹ Okin Industries sọ pe awọn…

Ka siwaju

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá mú àwọn òṣìṣẹ́ ọlọ́pàá mẹ́rin lẹ́yìn tí fídíò wọn jáde sórí ayélujára tó fi ẹ̀tanú ẹlẹ́yàmẹyà hàn, fa ìbínú gbígbóná janjan, tí wọ́n sì ń bèrè owo lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà tó ń bọ̀ láti UK.

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá mú àwọn òṣìṣẹ́ ọlọ́pàá mẹ́rin lẹ́yìn tí fídíò wọn jáde sórí ayélujára tó fi ẹ̀tanú ẹlẹ́yàmẹyà hàn, fa…

Ka siwaju

A wá láti ṣiṣẹ́, kì í ṣe láti kú’: Àwọn òṣìṣẹ́ ọmọ Nàìjíríà márùn-ún tí wọ́n di ẹni tí ó di mọ́ra ní ilẹ̀ òkèèrè ń bẹ̀bẹ̀ fún ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ ìjọba Tinubu lẹ́yìn tí ẹlẹgbẹ́ wọn kan kú ní ilé-iṣẹ́ kan ní orílẹ̀ èdè Iraq.

A wá láti ṣiṣẹ́, kì í ṣe láti kú’: Àwọn òṣìṣẹ́ ọmọ Nàìjíríà márùn-ún tí wọ́n di ẹni tí ó…

Ka siwaju