Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ ikọ̀ Boko Haram tàbí lọ bá àwọn ọlọ́ṣà agbésùmọ́mí fún ijiroro ìpàdé àlàáfíà , gẹ́gẹ́ bí Jonathan àti Osinbajo ti ṣe pẹ̀lú àwọn ọlọ̀tẹ̀ oníjàgídíjàgan agbègbè Niger Delta (Niger Delta militants) .

Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ…

Ka siwaju

Àwọn olùkọ́ ní Ọ̀yọ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ wọn bí àníyàn ṣe ń pọ̀ sí lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ ti wọn ji gbé, Àwọn ilé ìwé ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ tún ti ṣí sílẹ̀ lónìí, bí Ẹgbẹ́ Àwọn Olùkọ́ ní Nàìjíríà ((NUT) ti kéde

Àwọn ilé ìwé gbogbogbò ní Ìpínlẹ̀ Oyo tún ṣí sílẹ̀ lónìí, bí Ẹgbẹ́ Àwọn Olùkọ́ ní Nàìjíríà ti kéde ní…

Ka siwaju

Alakoso Iléeṣẹ́ Ologun Amẹrikà ṣe abẹwo sí Nàìjíríà fún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ìlọṣíwájú tí ètò ààbò ati ajọṣepọ láàrin orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti Amẹrikà ní ìgbìyànjú láti kojú àwọn agbésùmọ́mí.

Alakoso Ologun Amẹrikà ṣe abewo sí Nàìjíríà fún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ìlọṣíwájú tí ètò ààbò ati ajọṣepọ láàrin orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti…

Ka siwaju