Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ ikọ̀ Boko Haram tàbí lọ bá àwọn ọlọ́ṣà agbésùmọ́mí fún ijiroro ìpàdé àlàáfíà , gẹ́gẹ́ bí Jonathan àti Osinbajo ti ṣe pẹ̀lú àwọn ọlọ̀tẹ̀ oníjàgídíjàgan agbègbè Niger Delta (Niger Delta militants) .

Sheikh Gumi bèrè ìdí tí kò fi sí òṣìṣẹ́ Ìjọba Tinubu kankan tí ó ti lọ pàdé awọn ọmọ ẹgbẹ…

Ka siwaju

Ìjọba Nàìjíríà ya owó tó tó bíi bílíọ̀nù mẹ́jọ àti mílíọ̀nù márùndínláàádọ́ta (N8.05B)sọ́tọ̀ láti kọ́ tàbí ṣe àtúnṣe àwọn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́sálásí láàrin àkókò tí orílẹ̀-èdè náà dojú kọ ìṣòro gbèsè.

Ìjọba Nàìjíríà ya owó tó tó bíi bílíọ̀nù mẹ́jọ àti mílíọ̀nù márùndínláàádọ́ta (N8.05B)sọ́tọ̀ láti kọ́ tàbí ṣe àtúnṣe àwọn ṣọ́ọ̀ṣì…

Ka siwaju