Skip to content
  • Tuesday, 30 June 2026
  • 3:25 pm
  • Tẹle wa
ÀṢÀKẸ́ NEWS
  • Ile
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • Ẹ̀KỌ́ ÈDÈ YORÙBÁ
  • Home
  • Ìjọba Nàìjíríà ti mú 327 àwọn Awakùsà tó ń wa kùṣà lọ́nà tí kò bófin mú, pẹ̀lú àwọn afurasí àjèjì ọmọ ilẹ̀ òkèèrè tó ń lo àwọn agbésùnmọ̀mí láti wa kùṣà nínú Nàìjíríà.
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Ìjọba Nàìjíríà ti mú 327 àwọn Awakùsà tó ń wa kùṣà lọ́nà tí kò bófin mú, pẹ̀lú àwọn afurasí àjèjì ọmọ ilẹ̀ òkèèrè tó ń lo àwọn agbésùnmọ̀mí láti wa kùṣà nínú Nàìjíríà.

Asake May 15, 2026 0

ÀṢÀKẸ́ TV NEWS : Ìjọba Nàìjíríà ti Mu 327 Àwọn Awakùsà tó ń wa kùṣà lọ́nà tí kò bófin mú…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ààrẹ Tinubu rán gbákejì rẹ̀ Kashim Shettima lọ sí Ondo fún ti ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́rùn-ún ọdún DR. Reuben Fasoranti.

Asake May 11, 2026 0

Igbákejì Ààrẹ Nàìjíríà Kashim Shettima dé sí Ondo fún ti ayẹyẹ ọgọ́rùn-ún ọdún ọjọ́ ìbí Reuben Fasoranti. Igbákejì orílẹ̀ èdè…

Ka siwaju
ÌṢÈLÚ

Peter obi lára àwọn oludije fún ipò Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ti kéde ìfipòslẹ̀ rẹ̀ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú African Democratic Congress ADC.

Asake May 3, 2026 0

Peter obi ọ̀kan lára àwọn Oludije fún ipo Ààrẹ Nàìjíríà, ti kéde ifiposile re nínú ẹgbẹ́ òṣèlú African Democratic Congress…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn ẹlẹ́ṣọ àbò Aṣọ́gbó ti farapa yannayanna,Won pa ènìyàn méjì, tí wọ́n sì tún jí àwọn aráàlú gbé lọ ní ọsan gangan nígbà tí àwọn agbésùnmọ̀mí kọlù Oko Erese oro- àgọ́, Babanla Kwara.

Asake Apr 29, 2026 0

Awọn ará ìlú ti o ba oníròyìn sọrọ sọ pe ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé ni ọsan ọjọ ìṣẹ́gun, ọjọ́ kejìdnlogbon oṣù…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀sun ti rọ Ọba Gbenga Oloyede tìlú Ipetumodu lóye, látàrí ẹ̀sùn jìbìtì owó COVID19 tí ó gbé ọba lọ ẹ̀wọ̀n L’ámẹ́ríkà.

Asake Apr 28, 2026 0

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀sun ti gbé Ọba Gbenga Oloyede kúrò lórí ìtẹ́ ọba gẹ́gẹ́ bí Apetumodu ti Ipetumodu ni ìjọba ìbílẹ̀…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí ṣe ìkọlù sí ìjọba ìbílẹ̀ Gombi Adamawa, wọ́n pa ènìyàn 29.

Asake Apr 28, 2026 0

Gomina ìpínlẹ̀ Adamawa Ahmadu Fintiri ti fi idi rẹ ìkọlù náà mulẹ pe ko din ju eniyan 29 ni wọn…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn mẹta :Musa Ajibola, Umaru Hassan, Mohammed Hassan tó jí Marian Remi gbé ní Ido Ìbàdàn.

Asake Apr 23, 2026 0

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn mẹta :Musa Ajibola, Umaru Hassan, Mohammed Hassan tó jí Marian Remi gbé ní Ido Ìbàdàn. Iléeṣẹ́…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Oyedepo kéde ìdájọ́ lórí àwọn olugbowo to ń ṣe àtìlẹyìn fún àwọn agbésùnmọ̀mí

Asake Apr 23, 2026 0

Olùdásílè ti ìjọ Living Faith Church Worldwide, Bishop David Oyedepo, ti kéde ìdájọ́ lórí àwọn Adigunjalè,agbésùnmọ̀mí afẹ̀míṣòfòati awọn onígbọ̀wọ́ wọn.Oyedepo…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Abdrahman kéde pé òun yóò san N20milionu fún ẹnì kọ̀ọ̀kan àwọn ológun mẹta tí àwọn agbésùnmọ̀mí pa ni ọgbà ológun kemanji Kwara.

Asake Apr 21, 2026 0

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Abdrahman tí ṣe ìpinnu pé òun yóò san N20m fún ẹnì kọ̀ọ̀kan àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà mẹta…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí pa àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà mẹrin jí ọ̀pọ̀ ará ìlú gbé lọ, ni ọgbà ológun kemanji Kwara.

Asake Apr 20, 2026 0

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí da ìbọn bolẹ̀ yawọ ọgbà àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà tó wà ní kemanji ni ijoba ìbílẹ̀ kaiama Kwara,…

Ka siwaju

Posts pagination

1 2 3 4

Iroyin aipẹ

  • Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
  • Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
  • Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
  • Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
  • Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Iroyin to Nlo
Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
Jun 30, 2026
Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
Jun 29, 2026
Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Jun 29, 2026

Asọye aipẹ

  1. Katie1486 on Ìpayà bí iná ṣe jó ilé ìtajà ike tó wà ni old garage Osogbo tó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀sun.
  2. Hello from [your-website] on Bokoharam kéde pé àwọn fẹ́ ṣe ayẹyẹ ìparí ẹ̀kọ́ Al-Quran fún ọgọ́rùn-ún (100) nínú àwọn obìnrin àti àwọn ọmọ tí wọ́n jí gbé ní ìjọba Kaiama Kwara I to tí kẹ́kọ̀ọ́ yege ni àhámọ́ wọn.
  3. Asake on Ìjọba àpapọ̀ tí kó orúkọ àwọn ọmọ Nàìjíríà síta ,Tukur Mamu, Simon Njoku Ekpa, IPOB, àti àwọn gúrúpù12 mìíràn, tó ń ṣe ìrànlọ́wọ́ àti àtìlẹyìn fún àwọn agbésùnmọ̀mí.
  4. Asake on Ọwọ́ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó ti tẹ ọlọ́pàá tó n gba owó rìbá lọ́wọ́ àwọn awakọ̀, onikẹ̀kẹ́ maruwa, ọlọ́kadà ní Idimu L’eko.
  5. Asake on Ààrẹ Tinubu buwọ́lu N17bilionu láti ṣe àtìlẹyìn ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀,àti àwọn agbègbè ìsèlù 8,804 gbogbo orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Iroyin ti oti le Ti padanu
News Mart logo

Ni pa wa

Shagam
info@asakenews.com
+212 710-380820
Iroyin Tuntun
Orúkọ 104 àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ni kíkùn ni Iléeṣẹ́ ológun kọ síta pé wọ́n pàdánù pẹ̀lú àwọn ìbọn iṣẹ wọn ọ̀sé kan lẹ́hìn ìkọlù ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Iléeṣẹ́ ológun ọmọ Nàìjíríà kéde pe 104 ọmọ ogun ni won padanu ni ọsẹ kan lẹhin ikọlu ńlá ti Boko Haram ṣe sí Ibùdó ológun Borno.
Jun 30, 2026
Àwọn ọmọ ogún Nàìjíríà tí operations Hadin Kai (OPHK) tí ṣe àṣeyọrí gba àwọn ọmọ ilé ìwé mẹ́wàá tó ń ṣe ìdánwò Neco àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé sílẹ̀.
Jun 30, 2026
Àwọn agbésùmọ́mí ti dé ẹnu-ọ̀nà mi-Enoch Adeboye Olùdásílẹ̀ ìjọ Redeem sọ̀rọ̀.
Jun 29, 2026
Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fidi rẹ mulẹ pé àwọn Boko Haram ti jí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ to ń kọ ìdánwò Neco gbe lọ ,tí wọ́n sì pa awọn olùkọ́ nínú ìkọlù tó wáyé ní Borno.
Jun 29, 2026
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Forukọsilẹ Fun Iwe Iroyin Wa

Se alabapin si iwe iroyin wa lati gba awọn nkan tuntun wa lesekese!

Copyright © 2026 Asake News | Design by Yaagboyaaju Tech

  • Home
  • About
  • Blog
  • Contact