Skip to content
  • Sunday, 16 August 2026
  • 8:12 pm
  • Tẹle wa
ÀṢÀKẸ́ NEWS
  • Ile
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • Ẹ̀KỌ́ ÈDÈ YORÙBÁ
  • Home
  • Àwọn ẹlẹ́ṣọ àbò Aṣọ́gbó ti farapa yannayanna,Won pa ènìyàn méjì, tí wọ́n sì tún jí àwọn aráàlú gbé lọ ní ọsan gangan nígbà tí àwọn agbésùnmọ̀mí kọlù Oko Erese oro- àgọ́, Babanla Kwara.
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn ẹlẹ́ṣọ àbò Aṣọ́gbó ti farapa yannayanna,Won pa ènìyàn méjì, tí wọ́n sì tún jí àwọn aráàlú gbé lọ ní ọsan gangan nígbà tí àwọn agbésùnmọ̀mí kọlù Oko Erese oro- àgọ́, Babanla Kwara.

Asake Apr 29, 2026 0

Awọn ará ìlú ti o ba oníròyìn sọrọ sọ pe ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé ni ọsan ọjọ ìṣẹ́gun, ọjọ́ kejìdnlogbon oṣù…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn agbébọn yawọ ilé ìjọsìn Christ Apostolic church Eda Oniyo ní ìpínlẹ̀ Èkìtì, wón pa Pásítọ̀ ìjọ, wọ́n jí ọ̀pọ̀lọpọ̀ olùjọsìn gbé lọ.Ní dédé ago mẹ́jọ àbọ̀ àṣálẹ́8:30pm, ọjọ́ ìṣẹ́gun .

Asake Apr 29, 2026 0

Àwọn agbébọn yawọ ilé ìjọsìn Christ Apostolic church Eda Oniyo ní ìpínlẹ̀ Èkìtì, wón pa Pásítọ̀ ìjọ, wọ́n jí ọ̀pọ̀lọpọ̀…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí ti jí ọ̀gbẹ́ni Bamsa Remilekun Daniel gbé nínú oko rẹ̀ ni Egbe Ìjọba ìbílẹ̀ Yagba West ilẹ̀ Okun ìpínlẹ̀ Kogi.

Asake Apr 29, 2026 0

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí ti jí Ọgbẹni Bamsa Remilekun Daniel gbé nínú oko rẹ̀ ni Ègbé okun land. Ìròyìn fidi e mule…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Arábìnrin Shifawu Alabi ẹni Àádọ́rin Ọdún tó sọnù ni ọjà ọba Ìbàdàn ni wọ́n rí ní Ọ̀sun iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ ọ̀sun ló kéde rẹ̀.

Asake Apr 27, 2026 0

Arábìnrin ìyá àgbàlagbà kan ẹni Àádọ́rin Ọdún Shifawu Alabi tí ó sọnu tí àwọn ẹbí ń wá ní Ọjà ọba…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí JNIM pa ọ̀gá ológun ni Mali, lẹ́yìn tí wọ́n ṣe ìkọlù sí agbègbè Kidal.

Asake Apr 26, 2026 0

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí pa ọ̀gá ológun ni Mali, lẹ́yìn tí wọ́n ṣe ìkọlù sí agbègbè Kidal. Awọn ológun ti Mali ni…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ìjọba àpapọ̀ tí ṣe àgbékalè, àfihàn igbimọ ti yóò ṣe atunyẹwo,àti ṣe àlàyé àwọn ile-iṣẹ ètò ààbò Naijiria.

Asake Apr 24, 2026 0

Ìjọba Àpapọ̀ tíì ṣe ifilọlẹ igbimọ laarin minisita kan lati ṣe atunyẹwo afikun ati isọdọtun ti ijọba apapo, ipinlẹ, àti…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn mẹta :Musa Ajibola, Umaru Hassan, Mohammed Hassan tó jí Marian Remi gbé ní Ido Ìbàdàn.

Asake Apr 23, 2026 0

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn mẹta :Musa Ajibola, Umaru Hassan, Mohammed Hassan tó jí Marian Remi gbé ní Ido Ìbàdàn. Iléeṣẹ́…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ

Oluremi Tinubu sọ pé gbogbo àgbáyé gbọ́dọ̀ jáwọ́ nínú kíka àìṣedédé ètò ààbò orílẹ̀ èdè.

Asake Apr 23, 2026 0

Gbogbo àgbáyé gbọ́dọ̀ jáwọ́ nínú kíka àìṣedédé ètò ààbò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Sen. Oluremi Tinubu, àyà Aarẹ Bola Ahmed Tinubu ti…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Abdrahman kéde pé òun yóò san N20milionu fún ẹnì kọ̀ọ̀kan àwọn ológun mẹta tí àwọn agbésùnmọ̀mí pa ni ọgbà ológun kemanji Kwara.

Asake Apr 21, 2026 0

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Abdrahman tí ṣe ìpinnu pé òun yóò san N20m fún ẹnì kọ̀ọ̀kan àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà mẹta…

Ka siwaju
ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí pa àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà mẹrin jí ọ̀pọ̀ ará ìlú gbé lọ, ni ọgbà ológun kemanji Kwara.

Asake Apr 20, 2026 0

Àwọn Agbéṣùmọ̀mí da ìbọn bolẹ̀ yawọ ọgbà àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà tó wà ní kemanji ni ijoba ìbílẹ̀ kaiama Kwara,…

Ka siwaju

Posts pagination

1 … 8 9 10 11

Iroyin aipẹ

  • Ìdìbò ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Obìnrin oníwà-ipá jàǹdùnkú olóṣèlú kan tí wọ́n ń pè ní ‘Arugba’ halẹ̀ mọ́ àwọn olùdìbò pé òun yóò gé ìka ọwọ́ wọn tí wọn kò bá dìbò fún ẹgbẹ́ APC.
  • Ikọlu sí Agbẹnusọ Ile-igbimọ Ipinle Osun: Afurasi jẹwọ pe oludije ẹgbẹ APC, Eniade, lo gba oun láti pa a, o si tun jẹwọ pe oun yin ibọn lẹẹmeji.
  • Amnesty International tún rọ àwọn aláṣẹ ní Nàìjíríà láti bọ̀wọ̀ fún àwọn ẹ̀tọ́ ọmọ-ìlú nígbà ìdìbò Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
  • Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Àwọn ọlọ́pàá pe Sẹ́nátọ̀ Fadahunsi ti ẹgbẹ́ APC wá fún ìbéèrè lórí ọ̀rọ̀ ìhalẹ̀ láti pa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Accord.
  • Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Adeleke, fi ẹ̀sùn kan àwọn ọlọ́pàá pé wọ́n ní ètò láti mú àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord kí wọ́n sì fi wọ́n sẹ́wọ̀n ní Abuja títí tí ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun yóò fi parí.
Iroyin to Nlo
Ìdìbò ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Obìnrin oníwà-ipá jàǹdùnkú olóṣèlú kan tí wọ́n ń pè ní ‘Arugba’ halẹ̀ mọ́ àwọn olùdìbò pé òun yóò gé ìka ọwọ́ wọn tí wọn kò bá dìbò fún ẹgbẹ́ APC.
Aug 13, 2026
Ikọlu sí Agbẹnusọ Ile-igbimọ Ipinle Osun: Afurasi jẹwọ pe oludije ẹgbẹ APC, Eniade, lo gba oun láti pa a, o si tun jẹwọ pe oun yin ibọn lẹẹmeji.
Aug 13, 2026
Amnesty International tún rọ àwọn aláṣẹ ní Nàìjíríà láti bọ̀wọ̀ fún àwọn ẹ̀tọ́ ọmọ-ìlú nígbà ìdìbò Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
Aug 12, 2026
Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Àwọn ọlọ́pàá pe Sẹ́nátọ̀ Fadahunsi ti ẹgbẹ́ APC wá fún ìbéèrè lórí ọ̀rọ̀ ìhalẹ̀ láti pa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Accord.
Aug 12, 2026
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Adeleke, fi ẹ̀sùn kan àwọn ọlọ́pàá pé wọ́n ní ètò láti mú àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord kí wọ́n sì fi wọ́n sẹ́wọ̀n ní Abuja títí tí ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun yóò fi parí.
Aug 12, 2026

Asọye aipẹ

  1. ABDULRASAQ ADENIYI SOLIU on Àwọn ọkùnrin mẹ́jọ tí ọjọ́ orí wọn wà láàárín ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún sì méjìlélọ́gbọ̀n ni wọ́n fi ẹ̀sùn kàn lórí ètò láti kọlu ayẹyẹ UFC ti Trump ní Ilé Ààrẹ ni White House.
  2. Lewishow on Ìpayà bí iná ṣe jó ilé ìtajà ike tó wà ni old garage Osogbo tó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀sun.
  3. Timsothyemeri on Ìpayà bí iná ṣe jó ilé ìtajà ike tó wà ni old garage Osogbo tó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀sun.
  4. OLUFEMI OSHIKPOYA on Wọn pa ènìyàn kan, ọpọlọpọ farapa yannayanna bí Ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti Accord Party ṣe ja ni Osogbo.
  5. Alma1848 on Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ẹdo tẹ afurasí ajínigbé méjì, wọn gba ara ènìyàn tó ti jẹrà méjì padà.
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Iroyin ti oti le Ti padanu
News Mart logo

Ni pa wa

Shagam
info@asakenews.com
+212 710-380820
Iroyin Tuntun
Ìdìbò ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Obìnrin oníwà-ipá jàǹdùnkú olóṣèlú kan tí wọ́n ń pè ní ‘Arugba’ halẹ̀ mọ́ àwọn olùdìbò pé òun yóò gé ìka ọwọ́ wọn tí wọn kò bá dìbò fún ẹgbẹ́ APC.
Aug 13, 2026
Ikọlu sí Agbẹnusọ Ile-igbimọ Ipinle Osun: Afurasi jẹwọ pe oludije ẹgbẹ APC, Eniade, lo gba oun láti pa a, o si tun jẹwọ pe oun yin ibọn lẹẹmeji.
Aug 13, 2026
Amnesty International tún rọ àwọn aláṣẹ ní Nàìjíríà láti bọ̀wọ̀ fún àwọn ẹ̀tọ́ ọmọ-ìlú nígbà ìdìbò Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
Aug 12, 2026
Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun: Àwọn ọlọ́pàá pe Sẹ́nátọ̀ Fadahunsi ti ẹgbẹ́ APC wá fún ìbéèrè lórí ọ̀rọ̀ ìhalẹ̀ láti pa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Accord.
Aug 12, 2026
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Adeleke, fi ẹ̀sùn kan àwọn ọlọ́pàá pé wọ́n ní ètò láti mú àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord kí wọ́n sì fi wọ́n sẹ́wọ̀n ní Abuja títí tí ìdìbò ìpínlẹ̀ Osun yóò fi parí.
Aug 12, 2026
Awọn ẹka
  • ÀWỌN ÌRÒYÌN TÍ Ó NÍPA
  • Ere Idaraya
  • ÌGBÉSÍ AYÉ
  • ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
  • ÌRÒYÌN TÓ Ń LỌ
  • ÌṢÈLÚ
  • Uncategorized
Forukọsilẹ Fun Iwe Iroyin Wa

Se alabapin si iwe iroyin wa lati gba awọn nkan tuntun wa lesekese!

Copyright © 2026 Asake News | Design by Yaagboyaaju Tech

  • Home
  • About
  • Blog
  • Contact